1
SAMUẸLI KINNI 4:18
Yoruba Bible
Nígbà tí ọkunrin náà fẹnu kan àpótí Ọlọ́run, Eli ṣubú sẹ́yìn lórí àpótí tí ó jókòó lé ní ẹnu ọ̀nà, ọrùn rẹ̀ ṣẹ́, ó sì kú, nítorí pé ó ti di arúgbó, ó sì sanra. Ogoji ọdún ni Eli fi ṣe adájọ́ ní ilẹ̀ Israẹli.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí SAMUẸLI KINNI 4:18
2
SAMUẸLI KINNI 4:21
Ó bá sọ ọmọ náà ní Ikabodu, ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, “Ògo Ọlọrun ti fi Israẹli sílẹ̀.” Nítorí pé wọ́n ti gba àpótí Ọlọrun ati pé baba ọkọ rẹ̀ ati ọkọ rẹ̀ ti kú.
Ṣàwárí SAMUẸLI KINNI 4:21
3
SAMUẸLI KINNI 4:22
Ó ní, “Ògo Ọlọrun ti fi Israẹli sílẹ̀, nítorí pé wọ́n ti gbé àpótí Ọlọrun lọ.”
Ṣàwárí SAMUẸLI KINNI 4:22
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò