1
Esteri 1:1
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Èyí ni ohun tó ṣẹlẹ̀ ní ìgbà Ahaswerusi, tí ó jẹ ọba lórí ẹ̀tàdínláàdóje ìletò bẹ̀rẹ̀ láti India títí ó fi dé Etiopia.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Esteri 1:1
2
Esteri 1:12
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ìránṣẹ́ jẹ́ iṣẹ́ ọba, ayaba Faṣti kọ̀ láti wá. Nígbà náà ni ọba bínú gidigidi, ìbínú náà sì pọ̀ jọjọ.
Ṣàwárí Esteri 1:12
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò