1
Esteri 3:6
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Síbẹ̀ kò mọ irú ènìyàn tí Mordekai jẹ́, ó kẹ́gàn láti pa Mordekai nìkan. Dípò bẹ́ẹ̀ Hamani ń wá láti pa gbogbo ènìyàn Mordekai run, àwọn Júù jákèjádò gbogbo ìjọba Ahaswerusi.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Esteri 3:6
2
Esteri 3:2
Gbogbo àwọn ìjòyè ọba tí ó wà ní ẹnu-ọ̀nà ọba wọn kúnlẹ̀ wọ́n sì fi ọlá fun Hamani, nítorí ọba ti pàṣẹ èyí nípa tirẹ̀. Ṣùgbọ́n Mordekai kò ní kúnlẹ̀ tàbí bu ọlá fún un.
Ṣàwárí Esteri 3:2
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò