1
Eksodu 25:8-9
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
“Nígbà náà ni ìwọ yóò jẹ́ kí wọn kọ́ ibi mímọ́ fún mi. Èmi yóò sì máa gbé ní àárín wọn. Gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí ti mo fihàn ọ́, nípa àpẹẹrẹ àgọ́, àti àpẹẹrẹ gbogbo ohun èlò inú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin kí ó sì ṣe é.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Eksodu 25:8-9
2
Eksodu 25:2
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọn mú ọrẹ wá fún mi, ìwọ yóò gba ọrẹ náà fún mi ni ọwọ́ ọkùnrin kọ̀ọ̀kan ti ọkàn rẹ bá fẹ́ láti fi fún mi.
Ṣàwárí Eksodu 25:2
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò