Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

ISIKIẸLI 12:28

ISIKIẸLI 12:28 YCE

Nítorí náà, wí fún wọn pé: mo ní n kò ní fi ọ̀rọ̀ mi falẹ̀ mọ́, ṣugbọn ohun tí mo bá sọ yóo ṣẹ. Èmi OLUWA Ọlọrun ni mo wí bẹ́ẹ̀.”