Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

ISIKIẸLI 18:21

ISIKIẸLI 18:21 YCE

“Ṣugbọn bí eniyan burúkú bá yipada kúrò ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ń dá, tí ó ń pa òfin mi mọ́, tí ó ń ṣe ohun tí ó tọ́, tí ó sì bá òfin mu, dájúdájú yóo yè ni, kò ní kú.