Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

JOẸLI 2:28

JOẸLI 2:28 YCE

“Lẹ́yìn náà, nígbà tí ó bá yá, n óo tú ẹ̀mí mi jáde sára gbogbo eniyan, àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin yín yóo máa sọ àsọtẹ́lẹ̀, àwọn àgbààgbà yín yóo máa lá àlá, àwọn ọdọmọkunrin yín yóo sì máa ríran.