Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

JOṢUA 21:43

JOṢUA 21:43 YCE

Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ tí ó ti búra fún àwọn baba wọn. Lẹ́yìn tí wọ́n gba ilẹ̀ náà tán, wọ́n ń gbé ibẹ̀.