ÌFIHÀN 15:4

ÌFIHÀN 15:4 YCE

Ta ni kò ní bẹ̀rù rẹ, Oluwa? Ta ni kò ní fi ògo fún orúkọ rẹ? Nítorí ìwọ nìkan ni ó pé, nítorí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo wá, wọn yóo júbà níwájú rẹ, nítorí òdodo rẹ farahàn gbangba.”