Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

1 Kronika 29:11

1 Kronika 29:11 BMYO

Tìrẹ Olúwa ni títóbi àti agbára pẹ̀lú ìyìn àti ọláńlá àti dídán, nítorí tí gbogbo nǹkan ní ọ̀run àti ayé jẹ́ tìrẹ. Tìrẹ Olúwa ni ìjọba; a gbé ọ ga gẹ́gẹ́ bí orí lórí ohun gbogbo.