Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Esekiẹli 11:17

Esekiẹli 11:17 BMYO

“Nítorí náà, wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò kó wọn jọ kúrò láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, Èmi yóò sì fún wọn ní ilẹ̀ Israẹli padà.’