Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Esekiẹli 7:9

Esekiẹli 7:9 BMYO

Ojú mi kò ní i dá ọ sí, Èmi kò sì ní wò ọ́ pẹ̀lú àánú; èmi yóò san án fún ọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ àti fún gbogbo ìwà ìríra tí wà láàrín rẹ. “ ‘Nígbà náà ní ẹ o mọ̀ pé Èmi Olúwa lo kọlù yín.