Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Joṣua 21:43

Joṣua 21:43 BMYO

Báyìí ni Olúwa fún Israẹli ní gbogbo ilẹ̀ tí ó ṣèlérí láti fi fún àwọn baba ńlá wọn. Nígbà tí wọ́n sì gbà á tan wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.