Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Obadiah 1:15

Obadiah 1:15 BMYO

“Nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ etílé lórí gbogbo àwọn kèfèrí. Bí ìwọ ti ṣe, bẹ́ẹ̀ ni a ó ṣe sí ìwọ náà; ẹ̀san rẹ yóò sì yípadà sí orí ara rẹ.