Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Ṣe àfiwé gbogbo èyà

I. Kro 16:10YBCV(Bibeli Mimọ)

Ẹ ma ṣogo li orukọ rẹ̀ mimọ́; jẹ ki ọkàn awọn ti nwá Oluwa ki o yọ̀.

I. Kro 16:10BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)

Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́; jẹ kí ọkàn àwọn tí ó yin OLúWA kí ó yọ̀.

I. Kro 16:10YCE(Yoruba Bible)

Ẹ máa fi orúkọ rẹ̀ ṣògo, kí ọkàn àwọn tí wọn ń sin OLUWA kún fún ayọ̀.