Ṣe àfiwé gbogbo èyà
I. Kro 28:10YBCV(Bibeli Mimọ)
Wò o nisisiyi: nitori Oluwa ti yàn ọ lati kọ́ ile kan fun ibi mimọ́, mura le, ki iwọ si ṣe e.
I. Kro 28:10BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)
Gbèrò báyìí nítorí tí OLúWA ti yàn ọ́ láti kọ́ ilé OLúWA gẹ́gẹ́ bí ilé tí a yà sí mímọ́ fún OLúWA. Jẹ́ alágbára kí ó sì ṣe iṣẹ́ náà.”
I. Kro 28:10YCE(Yoruba Bible)
Kíyèsára, nítorí pé OLUWA ti yàn ọ́ láti kọ́ ilé kan tí yóo jẹ́ ibi mímọ́, ṣe gírí, kí o sì kọ́ ọ.”
Pín
I. Kro 28YCE