Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Ṣe àfiwé gbogbo èyà

II. A. Ọba 12:2YBCV(Bibeli Mimọ)

Jehoaṣi si ṣe eyiti o tọ́ li oju Oluwa li ọjọ rẹ̀ gbogbo ninu eyiti Jehoiada alufa nkọ́ ọ.

II. A. Ọba 12:2BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)

Jehoaṣi ṣe ohun tí ó tọ́ ní ojú OLúWA ní gbogbo ọdún tí Jehoiada àlùfáà fi àṣẹ fún un.

II. A. Ọba 12:2YCE(Yoruba Bible)

Ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ ó ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA nítorí pé Jehoiada alufaa ń tọ́ ọ sọ́nà.