Ṣe àfiwé gbogbo èyà
Hos 11:1YBCV(Bibeli Mimọ)
NIGBATI Israeli wà li ọmọde, nigbana ni mo fẹ́ ẹ, mo si pè ọmọ mi lati Egipti jade wá.
Pín
Hos 11YBCVHos 11:1BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)
“Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀, mo sì pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.
Pín
Hos 11BMYOHos 11:1YCE(Yoruba Bible)
OLUWA ní, “Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọde, mo fẹ́ràn rẹ̀, láti ilẹ̀ Ijipti ni mo sì ti pe ọmọ mi jáde.
Pín
Hos 11YCE