Ṣe àfiwé gbogbo èyà
Joṣ 10:8YBCV(Bibeli Mimọ)
OLUWA si wi fun Joṣua pe, Má ṣe bẹ̀ru wọn: nitoriti mo ti fi wọn lé ọ lọwọ; ki yio sí ọkunrin kan ninu wọn ti yio le duro niwaju rẹ.
Pín
Joṣ 10YBCVJoṣ 10:8BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)
OLúWA sì sọ fún Joṣua pé, “Má ṣe bẹ̀rù wọn, Mo ti fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́. Kò sí ẹnikẹ́ni nínú wọn ti yóò lè dojúkọ ọ́.”
Pín
Joṣ 10BMYOJoṣ 10:8YCE(Yoruba Bible)
OLUWA wí fún Joṣua pé, “Má bẹ̀rù wọn, nítorí pé mo ti fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́. Ẹnikẹ́ni ninu wọn kò ní lè ṣẹgun rẹ.”
Pín
Joṣ 10YCE