Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Ṣe àfiwé gbogbo èyà

O. Daf 129:4YBCV(Bibeli Mimọ)

Olododo li Oluwa: o ti ke okùn awọn enia buburu kuro.

O. Daf 129:4BMYO(Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)

Olódodo ni OLúWA: ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”

O. Daf 129:4YCE(Yoruba Bible)

Ṣugbọn olódodo ni OLUWA, ó ti gé okùn àwọn eniyan burúkú.