1
JEREMAYA 6:16
Yoruba Bible
OLUWA ní, “Ẹ lọ dúró ní oríta kí ẹ wo òréré, ẹ bèèrè àwọn ọ̀nà àtijọ́, níbi tí ọ̀nà dáradára wà, kí ẹ sì máa tọ̀ ọ́. Kí ẹ lè ní ìsinmi.” Ṣugbọn wọ́n kọ̀, wọ́n ní, “A kò ní tọ ọ̀nà náà.”
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí JEREMAYA 6:16
2
JEREMAYA 6:14
Wọn kò wẹ egbò àwọn eniyan mi jiná, wọ́n ń kígbe pé: ‘Alaafia ni, alaafia ni’, nígbà tí kò sí alaafia.
Ṣàwárí JEREMAYA 6:14
3
JEREMAYA 6:19
Gbọ́! Ìwọ ilẹ̀; n óo fa ibi lé àwọn eniyan wọnyi lórí, wọn óo jèrè èso ìwà burúkú wọn; nítorí pé wọn kò fetí sí ọ̀rọ̀ mi, wọ́n sì ti tàpá sí òfin mi.
Ṣàwárí JEREMAYA 6:19
4
JEREMAYA 6:10
Mo ní, “Ta ni kí n bá sọ̀rọ̀, tí yóo gbọ́? Ta ni kí n kìlọ̀ fún tí yóo gbà? Etí wọn ti di, wọn kò lè gbọ́ràn mọ́. Ọ̀rọ̀ OLUWA ń rùn létí wọn, wọn kò fẹ́ gbọ́ mọ́.
Ṣàwárí JEREMAYA 6:10
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò