1
2 Samuẹli 9:7
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Dafidi sì wí fún un pé, “Má ṣe bẹ̀rù, nítorí pé nítòótọ́ èmi ó ṣe oore fún ọ nítorí Jonatani baba rẹ, èmi ó sì tún fi gbogbo ilé Saulu baba rẹ fún ọ, ìwọ ó sì máa bá mi jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ mi.”
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí 2 Samuẹli 9:7
2
2 Samuẹli 9:1
Dafidi sì béèrè pé, ọ̀kan nínú àwọn ẹni tí ń ṣe ìdílé Saulu kù síbẹ̀ bí? Kí èmi lè ṣe oore fún un nítorí Jonatani.
Ṣàwárí 2 Samuẹli 9:1