1
Jeremiah 50:34
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
BMYO
Síbẹ̀, Olùràpadà wọn, Alágbára, OLúWA Ọlọ́run Alágbára ni orúkọ rẹ̀. Yóò sì gbe ìjà wọn jà, kí ó ba à lè mú wọn wá sinmi ní ilẹ̀ náà; ṣùgbọ́n kò sí ìsinmi fún àwọn tí ó ń gbé Babeli.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Jeremiah 50:34
2
Jeremiah 50:6
“Àwọn ènìyàn mi ti jẹ́ àgùntàn tí ó sọnù, àwọn olùṣọ́-àgùntàn wọn ti jẹ́ kí wọn ṣìnà, wọ́n ti jẹ́ kí wọn rìn lórí òkè wọ́n ti lọ láti orí òkè ńlá dé òkè kékeré, wọn ti gbàgbé ibùsùn wọn.
Ṣàwárí Jeremiah 50:6
3
Jeremiah 50:20
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni OLúWA wí, “À ó wá àìṣedéédéé ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli, ṣùgbọ́n a ki yóò rí ohun; àti ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a ki yóò sì rí mọ kankan nítorí èmi yóò dáríjì àwọn tí ó ṣẹ́kù tí mo dá sí.
Ṣàwárí Jeremiah 50:20