1
Numeri 9:23
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Nípa àṣẹ OLúWA ni wọ́n ń pa ibùdó wọn, nípa àṣẹ OLúWA náà sì ni wọ́n ń gbéra. Wọ́n gbọ́rọ̀ sí àṣẹ OLúWA ní ìbámu pẹ̀lú àṣẹ OLúWA láti ẹnu Mose.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Numeri 9:23
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò