NAHUMU Ọ̀rọ̀ Iṣaaju
Ọ̀rọ̀ Iṣaaju
Ìwé Nahumu jẹ́ àkọsílẹ̀ ewì ìdùnnú tí Wolii Nahumu fi sọ ìran tí ó rí nígbà tí ogun kó ìlú Ninefe, tí ó jẹ́ olú-ìlú ilẹ̀ Asiria, ọ̀tá àwọn ọmọ Israẹli. Ní nǹkan bíi ẹẹdẹgbẹrin ọdún kí á tó bí Oluwa wa (7th Century B.C.) ni ogun kó Ninefe tí a sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí. Àwọn ọmọ Israẹli sì gbàgbọ́ pé ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Ninefe náà jẹ́ ìjẹníyà láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun nítorí ìwà ìkà ati ìgbéraga Ninefe.
Àwọn Ohun tí ó wà ninu Ìwé yìí ní Ìsọ̀rí-ìsọ̀rí
Ìdájọ́ lórí Ninefe 1:1-15
Ìṣubú Ninefe 2:1–3:19
Àwon tá yàn lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí:
NAHUMU Ọ̀rọ̀ Iṣaaju: YCE
Ìsàmì-sí
Pín
Daako
![None](/_next/image?url=https%3A%2F%2Fimageproxy.youversionapistaging.com%2F58%2Fhttps%3A%2F%2Fweb-assets.youversion.com%2Fapp-icons%2Fyo.png&w=128&q=75)
Ṣé o fẹ́ fi àwọn ohun pàtàkì pamọ́ sórí gbogbo àwọn ẹ̀rọ rẹ? Wọlé pẹ̀lú àkántì tuntun tàbí wọlé pẹ̀lú àkántì tí tẹ́lẹ̀
Bible Society of Nigeria © 1900/2010