Má yọ̀ nígbà tí ọ̀tá rẹ bá ṣubú, má sì jẹ́ kí inú rẹ dùn bí ó bá kọsẹ̀, kí OLUWA má baà bínú sí ọ tí ó bá rí ọ, kí ó sì yí ojú ibinu rẹ̀ pada kúrò lára ọ̀tá rẹ.
Kà ÌWÉ ÒWE 24
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: ÌWÉ ÒWE 24:17-18
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò