Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

2 Ọba 19:15

2 Ọba 19:15 BMYO

Hesekiah gbàdúrà sí Olúwa: “Olúwa Ọlọ́run Israẹli, tí ń gbé ní àárín àwọn kérúbù, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run lórí gbogbo ìjọba tí ó wà láyé, ìwọ ti dá ọ̀run àti ayé.