Àmì Ìdánimọ̀ Ohun-èlò Bíbélì
Ṣe Àwárí

Ẹkún Jeremiah 1:20

Ẹkún Jeremiah 1:20 BMYO

“Olúwa, wò ó, bí mo ti wà nínú ìnira! Tí mo sì ń jẹ̀rora nínú mi, ìdààmú dé bá ọkàn mi nítorí pé a ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi gidigidi. Ní gbangba ni idà ń parun; ikú wà nínú ilé pẹ̀lú.